Online Bible

- Advertisements -




Daniẹli 2:31 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

31 “Ìwọ ọba ń wo, ère ńlá kan tí ó dúró níwájú rẹ, ère náà ga, ó sì dára láti wò, ìrísí i rẹ̀ ba ni lẹ́rù jọjọ.

See the chapter Copy

Yoruba Bible

31 “Kabiyesi, o rí ère kan níwájú rẹ ní ojúran, ère yìí tóbi gan-an, ó mọ́lẹ̀, ó ń dán, ìrísí rẹ̀ sì bani lẹ́rù.

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

31 Iwọ ọba nwò, si kiyesi, ere nla kan. Ere giga yi, ti didan rẹ̀ pọ̀ gidigidi, o duro niwaju rẹ, ìrí rẹ̀ si ba ni lẹ̀ru gidigidi.

See the chapter Copy




Daniẹli 2:31

Follow us:

Advertisements


Advertisements