Online Bible

- Advertisements -




Daniẹli 2:12 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

12 Èyí mú kí ọba bínú, ó sì kanra, nítorí náà ó pàṣẹ kí a pa gbogbo àwọn amòye Babeli run.

See the chapter Copy

Yoruba Bible

12 Nítorí náà inú ọba ru, ó sì bínú gidigidi, ó bá pàṣẹ pé kí wọ́n pa gbogbo àwọn ọlọ́gbọ́n Babiloni run.

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

12 Nitori ọ̀ran yi ni inu ọba fi bajẹ, o si binu gidigidi, o si paṣẹ pe ki nwọn ki o pa gbogbo awọn amoye Babeli run.

See the chapter Copy




Daniẹli 2:12

Follow us:

Advertisements


Advertisements