Online Bible

- Advertisements -




Daniẹli 1:16 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

16 Bẹ́ẹ̀ ni olùṣọ́ mú oúnjẹ àdídùn àti wáìnì tí ó yẹ kí wọ́n mu kúrò, ó sì fún wọn ní ewébẹ̀ dípò rẹ̀.

See the chapter Copy

Yoruba Bible

16 Nítorí náà, ẹni tí ń tọ́jú wọn bẹ̀rẹ̀ sí fún wọn ní ẹ̀wà, dípò oúnjẹ aládùn tí wọn ìbá máa jẹ ati ọtí tí wọn ìbá máa mu.

See the chapter Copy

Bibeli Mimọ

16 Bẹ̃ni olutọju mu onjẹ adidùn wọn kuro, ati ọti-waini ti nwọn iba mu, o si fun wọn li ẹ̀wa.

See the chapter Copy




Daniẹli 1:16

Follow us:

Advertisements


Advertisements