Online Bible

- Advertisements -




Numeri 5:23 - Bibeli Mimọ

23 Ki alufa ki o si kọ egún yi sinu iwé, ki o si fi omi kikorò na wẹ̀ ẹ nù:

See the chapter Copy

Yoruba Bible

23 “Lẹ́yìn èyí, kí alufaa kọ ègún yìí sinu ìwé, kí ó sì fọ̀ ọ́ sinu abọ́ omi kíkorò náà.

See the chapter Copy

Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

23 “ ‘Nígbà náà ni àlùfáà yóò kọ ègún yìí sínú ìwé kíká, yóò sì sìn ín sínú omi kíkorò náà.

See the chapter Copy




Numeri 5:23

Follow us:

Advertisements


Advertisements