Online Bibel

- Annoncer -




Rutu 1:15 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

15 Naomi wí pé, “Wò ó, arábìnrin rẹ ti padà lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn ènìyàn rẹ̀ àti òrìṣà rẹ̀, ìwọ náà padà pẹ̀lú rẹ̀.”

Se kapitlet Kopi

Yoruba Bible

15 Naomi bá sọ fún Rutu, ó ní, “Ṣé o rí i pé arabinrin rẹ ti pada sọ́dọ̀ àwọn eniyan rẹ̀ ati àwọn oriṣa rẹ̀, ìwọ náà pada, kí ẹ jọ máa lọ.”

Se kapitlet Kopi

Bibeli Mimọ

15 On si wipe, Kiyesi i, orogun rẹ pada sọdọ awọn enia rẹ̀, ati sọdọ oriṣa rẹ̀: iwọ pada tẹlé orogun rẹ.

Se kapitlet Kopi




Rutu 1:15

Følg os:

Annoncer


Annoncer