Online Bibel

- Annoncer -




Luku 1:59 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

59 Ó sì ṣe, ní ọjọ́ kẹjọ wọ́n wá láti kọ ọmọ náà nílà; wọ́n sì fẹ́ sọ orúkọ rẹ̀ ní Sekariah, gẹ́gẹ́ bí orúkọ baba rẹ̀.

Se kapitlet Kopi

Yoruba Bible

59 Nígbà tí ó di ọjọ́ kẹjọ, wọ́n wá láti kọ́ ọmọ náà ní ilà-abẹ́. Wọ́n fẹ́ sọ ọ́ ní Sakaraya, bí orúkọ baba rẹ̀.

Se kapitlet Kopi

Bibeli Mimọ

59 O si ṣe, ni ijọ kẹjọ nwọn wá lati kọ ọmọ na nila; nwọn si sọ orukọ rẹ̀ ni Sakariah, gẹgẹ bi orukọ baba rẹ̀.

Se kapitlet Kopi




Luku 1:59

Følg os:

Annoncer


Annoncer