Online Bibel

- Annoncer -




Luku 1:29 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

29 Ṣùgbọ́n ọkàn Maria kò lélẹ̀ nítorí ọ̀rọ̀ náà, ó sì rò nínú ara rẹ̀ pé, irú kíkí kín ni èyí.

Se kapitlet Kopi

Yoruba Bible

29 Nígbà tí Maria gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí, ara rẹ̀ kò balẹ̀, ó ń rò lọ́kàn rẹ̀ pé, irú kíkí wo nìyí?

Se kapitlet Kopi

Bibeli Mimọ

29 Ṣugbọn ọkàn rẹ̀ kò lelẹ nitori ọ̀rọ na, o si rò ninu ara rẹ̀ pe, irú kíki kili eyi.

Se kapitlet Kopi




Luku 1:29

Følg os:

Annoncer


Annoncer