Online Bibel

- Annoncer -




Luku 1:22 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

22 Nígbà tí ó sì jáde wá, òun kò le bá wọn sọ̀rọ̀. Wọn sì kíyèsi wí pé ó ti rí ìran nínú tẹmpili, ó sì ń ṣe àpẹẹrẹ sí wọn, nítorí tí ó yadi.

Se kapitlet Kopi

Yoruba Bible

22 Nígbà tí ó jáde, kò lè bá wọn sọ̀rọ̀. Wọ́n sì mọ̀ pé ó ti rí ìran ninu iyàrá Tẹmpili ni. Ó yadi, ọwọ́ ni ó fi ń ṣe àpèjúwe fún wọn.

Se kapitlet Kopi

Bibeli Mimọ

22 Nigbati o si jade, kò le fọhun si wọn: nwọn si woye pe o ri iran ninu tẹmpili: nitoriti o nṣe apẹrẹ si wọn, o si yà odi.

Se kapitlet Kopi




Luku 1:22

Følg os:

Annoncer


Annoncer