Online Bibel

- Annoncer -




Johanu 1:32 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

32 Nígbà náà ni Johanu jẹ́rìí sí i pé: “Mo rí Ẹ̀mí sọ̀kalẹ̀ láti ọ̀run wá bí àdàbà, tí ó sì bà lé e.

Se kapitlet Kopi

Yoruba Bible

32 Johanu tún jẹ́rìí pé, “Mo ti rí Ẹ̀mí tí ó sọ̀kalẹ̀ bí àdàbà láti ọ̀run tí ó bà lé e, tí ó sì ń bá a gbé.

Se kapitlet Kopi

Bibeli Mimọ

32 Johanu si jẹri, o wipe, mo ri Ẹmi sọkalẹ lati ọrun wá bi àdaba, o si bà le e.

Se kapitlet Kopi




Johanu 1:32

Følg os:

Annoncer


Annoncer