Online Bibel

- Annoncer -




Eksodu 1:20 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

20 Nítorí náà Ọlọ́run ṣàánú fún àwọn agbẹ̀bí náà, àwọn ọmọ Israẹli sì ń le sí i, wọ́n sì ń pọ̀ sí i jọjọ.

Se kapitlet Kopi

Yoruba Bible

20 Nítorí náà, Ọlọrun ṣe àwọn agbẹ̀bí náà dáradára; àwọn eniyan Israẹli ń pọ̀ sí i, wọ́n sì ń lágbára sí i.

Se kapitlet Kopi

Bibeli Mimọ

20 Nitorina Ọlọrun ṣe rere fun awọn iyãgbà na: awọn enia na si mbisi i, nwọn si di alagbara koko.

Se kapitlet Kopi




Eksodu 1:20

Følg os:

Annoncer


Annoncer