Ọbadiah 1:21 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní21 Àwọn tó ń gba ni là yóò sì gòkè Sioni wá láti jẹ ọba lé orí àwọn òkè Esau. Ìjọba náà yóò sì jẹ́ ti Olúwa. Viz kapitolaYoruba Bible21 Àwọn olùgbàlà yóo lọ láti Sioni, wọn yóo jọba lórí òkè Edomu; ìjọba náà yóo sì jẹ́ ti OLUWA.” Viz kapitolaBibeli Mimọ21 Awọn olugbala yio si goke Sioni wá lati ṣe idajọ oke Esau; ijọba na yio si jẹ ti Oluwa. Viz kapitola |