Online Bible

- Reklamy -




Daniẹli 2:8 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

8 Nígbà náà ni ọba sọ pé, “Èmi mọ̀ dájú wí pé ẹ̀yin fẹ́ fi àkókò ṣòfò nítorí pé ẹ̀yin ti mọ̀ pé nǹkan ti lọ ní orí mi:

Viz kapitola kopírovat

Yoruba Bible

8 Ọba dá wọn lóhùn pé, “Mo mọ̀ dájú pé ẹ kàn fẹ́ máa fi ọgbọ́n fi àkókò ṣòfò ni, nítorí ẹ ti mọ̀ pé bí mo ti wí ni n óo ṣe.

Viz kapitola kopírovat

Bibeli Mimọ

8 Ọba si dahùn o wi pe, emi mọ̀ dajudaju pe, ẹnyin fẹ mu akoko pẹ, nitoriti ẹnyin ri pe nkan na lọ li ori mi.

Viz kapitola kopírovat




Daniẹli 2:8

Následuj nás:

Reklamy


Reklamy