Numeri 5:23 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní23 “ ‘Nígbà náà ni àlùfáà yóò kọ ègún yìí sínú ìwé kíká, yóò sì sìn ín sínú omi kíkorò náà. Sien die hoofstukYoruba Bible23 “Lẹ́yìn èyí, kí alufaa kọ ègún yìí sinu ìwé, kí ó sì fọ̀ ọ́ sinu abọ́ omi kíkorò náà. Sien die hoofstukBibeli Mimọ23 Ki alufa ki o si kọ egún yi sinu iwé, ki o si fi omi kikorò na wẹ̀ ẹ nù: Sien die hoofstuk |