Aanlyn Bybel

- Advertensies -




Numeri 5:23 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

23 “ ‘Nígbà náà ni àlùfáà yóò kọ ègún yìí sínú ìwé kíká, yóò sì sìn ín sínú omi kíkorò náà.

Sien die hoofstuk Kopieer

Yoruba Bible

23 “Lẹ́yìn èyí, kí alufaa kọ ègún yìí sinu ìwé, kí ó sì fọ̀ ọ́ sinu abọ́ omi kíkorò náà.

Sien die hoofstuk Kopieer

Bibeli Mimọ

23 Ki alufa ki o si kọ egún yi sinu iwé, ki o si fi omi kikorò na wẹ̀ ẹ nù:

Sien die hoofstuk Kopieer




Numeri 5:23

Volg ons:

Advertensies


Advertensies