Aanlyn Bybel

- Advertensies -




Esteri 1:15 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

15 Ó béèrè pé, “Kí ni a lè ṣe sí ayaba Faṣti gẹ́gẹ́ bí òfin? Nítorí kò tẹríba fún àṣẹ ọba Ahaswerusi tí àwọn ìwẹ̀fà ọba sọ fún un.”

Sien die hoofstuk Kopieer

Yoruba Bible

15 Ọba bi wọ́n pé, “Gẹ́gẹ́ bí òfin, kí ni kí á ṣe sí Ayaba Faṣiti, nítorí ohun tí ọba pa láṣẹ, tí ó rán àwọn ìwẹ̀fà sí i pé kí ó ṣe kò ṣe é.”

Sien die hoofstuk Kopieer

Bibeli Mimọ

15 Pe, gẹgẹ bi ofin, Kini ki a ṣe si Faṣti ayaba, nitoriti on kò ṣe bi Ahaswerusi ọba ti paṣẹ fun u, lati ọwọ awọn ìwẹfa rẹ̀ wá?

Sien die hoofstuk Kopieer




Esteri 1:15

Volg ons:

Advertensies


Advertensies