Aanlyn Bybel

- Advertensies -




Eksodu 5:21 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

21 Wọn sì wí pé, “Kí Olúwa kí ó wò yín, kí ó sì ṣe ìdájọ́! Ẹ̀yin ti mú wa dàbí òórùn búburú fún Farao àti àwọn òṣìṣẹ́ rẹ̀, ẹ sì ti fún wọn ni idà láti fi pa wá.”

Sien die hoofstuk Kopieer

Yoruba Bible

21 “Ọlọrun ni yóo dájọ́ fún yín, ẹ̀yin tí ẹ sọ wá di ẹni ìríra níwájú Farao ati àwọn iranṣẹ rẹ̀, ẹ sì ti yọ idà lé wọn lọ́wọ́ kí wọ́n fi pa wá.”

Sien die hoofstuk Kopieer

Bibeli Mimọ

21 Nwọn si wi fun wọn pe, Ki OLUWA ki o wò nyin, ki o si ṣe idajọ; nitoriti ẹnyin mu wa di okú-õrùn li oju Farao, ati li oju awọn iranṣẹ rẹ̀, lati fi idá lé wọn lọwọ lati pa wa.

Sien die hoofstuk Kopieer




Eksodu 5:21

Volg ons:

Advertensies


Advertensies