Aanlyn Bybel

- Advertensies -




Eksodu 5:15 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

15 Nígbà náà ni àwọn alábojútó iṣẹ́ tí a yàn lára àwọn ọmọ Israẹli tọ Farao lọ láti lọ bẹ̀bẹ̀ pé, “Èéṣe tí ìwọ fi ọwọ́ líle mú àwa ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ báyìí?

Sien die hoofstuk Kopieer

Yoruba Bible

15 Àwọn tí wọ́n fi ṣe olórí láàrin àwọn ọmọ Israẹli bá ké tọ Farao lọ, wọ́n ní, “Kí ló dé tí o fi ń ṣe báyìí sí àwa iranṣẹ rẹ?

Sien die hoofstuk Kopieer

Bibeli Mimọ

15 Nigbana li awọn olori awọn ọmọ Israeli wá, nwọn si ke tọ̀ Farao wipe, Ẽṣe ti iwọ fi nṣe awọn iranṣẹ rẹ bayi?

Sien die hoofstuk Kopieer




Eksodu 5:15

Volg ons:

Advertensies


Advertensies