Aanlyn Bybel

- Advertensies -




Eksodu 1:19 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní

19 Àwọn agbẹ̀bí náà sì dá Farao lóhùn pé, “Àwọn obìnrin Heberu kò rí bí àwọn obìnrin Ejibiti, wọ́n ní agbára, wọ́n sì ti máa ń bí ọmọ kí àwọn agbẹ̀bí tó dé ọ̀dọ̀ wọn.”

Sien die hoofstuk Kopieer

Yoruba Bible

19 Wọ́n dá Farao lóhùn pé, “Àwọn obinrin Heberu yàtọ̀ sí àwọn obinrin Ijipti. Wọ́n lágbára, wọn a sì ti máa bímọ kí á tó dé ọ̀dọ̀ wọn.”

Sien die hoofstuk Kopieer

Bibeli Mimọ

19 Awọn iyãgbà si wi fun Farao pe, nitoriti awọn obinrin Heberu kò ri bi awọn obinrin Egipti; nitoriti ara yá wọn, nwọn a si ti bí ki awọn iyãgbà to wọle tọ̀ wọn lọ.

Sien die hoofstuk Kopieer




Eksodu 1:19

Volg ons:

Advertensies


Advertensies