Daniẹli 1:9 - Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní9 Ọlọ́run mú kí Daniẹli rí ojúrere àti àánú gbà láti ọwọ́ olórí àwọn ìwẹ̀fà, Sien die hoofstukYoruba Bible9 Ọlọrun jẹ́ kí Daniẹli bá ojurere ati àánú olórí àwọn ìwẹ̀fà náà pàdé. Sien die hoofstukBibeli Mimọ9 Ọlọrun sa ti mu Danieli ba ojurere ati iyọ́nu pade lọdọ olori awọn iwẹfa. Sien die hoofstuk |